Yoruba
-
Póópù Francis kò kú o
Ahesọ: Olumulo ikanni ibaraeniṣọrẹ Facebook sọ wípé oludari ìjọ mímọ́ àgùdà, póópù Francis ti jade láyé. Abajade iwadii: Irọ́ ni!…
Read More » -
Òdodo ọ̀rọ̀! Orílẹ́èdè Nàíjírìà ló ní ọkọ̀ ojú irin ayára bí àṣá tó sáré jùlọ ní ilẹ̀ Áfríkà
Ahesọ: Olumulo ikanni ibaraenisore Facebook sọ laipẹ yi pe orileede Nàíjírìà ló ní ọkọ̀ ojú irin ayára bí àṣá tó…
Read More » -
Ṣọ́ra ṣe, ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti ò fún ẹnikẹ́ni ní owó ìrànwọ́ Ramadan
Aheso: Oju opo kan lori ikanni Ibaraenisore, Ramadan Gift, sọ wipe ìjọba ń fún awon ọdọ Yoruba ni ẹ̀bùn egberun…
Read More » -
Ipa wo ni ìmọ́tótó eyín kó lara ìlera ọkàn?
Aheso: Olumulo ikanni Instagram kan sọ wípé ti ènìyàn ba kọ̀ lati fọ enu ni ale ki o to sun,…
Read More » -
Ìdírèé tí o kò gbọdọ̀ fún ènìyàn tó farapa nínú ìjàmbá lómi mu
Ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà, tí a bá rí ènìyàn to ni ìjàmbá ọkọ̀, wọ́n a máa bèèrè fun omi. Gẹgẹbi ènìyàn…
Read More » -
Ǹjẹ́ èèwọ̀ ni fún àwọn Mùsùlùmí ilẹ̀ Yorùbá lati pè’run ní Àríwá Nàìjíríà?
Àhesọ: Aṣàmúlò X kan sọ pé àwọn Mùsùlùmí Ilẹ̀ Yorùbá ni wọ́n fòfin de láti darí àdúrà ní Àríwá Nàìjíríà. …
Read More » -
Ṣe itọ ni won fi n se ìtọ́jú ojú pipọn, conjunctivitis?
Aheso: Olumulo ikanni ibaraenisore sọ wípé ènìyàn lè fi ìtọ àárọ̀ kùtùkùtù ṣe ìtọ́jú aarun conjunctivitis. Abajade iwadii: Irọ nla!…
Read More » -
Njẹ́ Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kejì lágbàáyé tó ní iye ènìyàn tó pọ̀ jùlọ, tí ń gbé pẹ̀lú HIV
Àhesọ: Nàìjíríà jẹ́ orílẹ̀-èdè kejì tó ní iye ènìyàn tó pọ̀ jùlọ, tí ń gbé pẹ̀lú HIV. Àbájáde Ìwádìí: Ìṣìnà.…
Read More » -
Àmì ẹ̀yẹ àgbáyé: Tani Kayọde Adewale, oludanilẹkọ imo isiro l’ede Yoruba?
Awọn Yoruba p’òwe, wọ́n ni bi a kò bá dẹ́kun ìgbìyànjú, bó pẹ́ bó yá akitiyan á dópin lọ́jọ́ kan,…
Read More » -
Ǹjẹ́ EFCC rí owó àti oògùn olóró n’ilé ọmọ El-Rufai, gẹ́gẹ́ bí aṣàmúlò Facebook ṣe sọ?
Àhesọ: Aṣàmúlò Facebook kan sọ pé EFCC ṣàwárí owó àti oògùn olóró ní ilé ọmọ El-Rufai, ní Kaduna. Àbájáde Ìwádìí: …
Read More »