08
Fact Check

Ǹjẹ́ àjọ NDLEA yan Naira Marley sípò aṣojú?

Elizabeth Ogunbamowo · 7 views · Oct 5, 2023

Awọn olumulo ẹ̀rọ alatagba ń fi abuku kan Náírà Marley àti ile-ise orin, Marlian Music, lórí ikú Mohbad. Bí awọn ọmọ orilẹ-ede Nàìjíríà ti n rọ awọn ẹṣọ aláàbò pé kí wọ́n ṣe ìwádìí to péye lórí ọrọ naa, àwọn ẹlòmíràn bu enu àtẹ́ lu NDLEA fún ibaṣepọ won pelu ọgbẹni Fasola (Naira Marley).